Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- GBV Killing Innocent Souls, Shattering Beautiful Ambitions, Ekiti Govt Laments
- EKITI NUT, HEAD-TEACHERS’ ASSOCIATION, OTHERS ENDORSE OYEBANJI FOR SECOND TERM
- Shun Violence, Division, Ekiti Govt Warns Communities Demanding Autonomy
- Governor Oyebanji Reaffirms Commitment to Citizens’ Economic Empowerment.
- Ekiti Schools to resume for 2024/2025 academic session on Tuesday