
Gómìnà Èkìtì, Ọ̀gbẹ́ni Bíọ́dún Oyèbánjí ti kí gbogbo Krìstíánì lónílé àtàlejò kú ọdún Àjínde Jésù Krístì Olúwa wa.
Bẹ́ẹ̀ ló képè wọ́n láti wo ìfẹ́ tí Krístì fihàn nípa fífi ẹ̀mí rẹ̀ lélẹ̀ fún ìdáríjì ẹ̀ṣẹ̀ aráyé, káwọn náà pẹ̀lú ní ìfẹ́ sí ọmọnìkéjì wa fún ìdàgbàsókè ìlú àtorílẹ̀ èdè.
- New Army formation takes off in Ekiti
- GOVERNOR OYEBANJI TO COMMISSION NEW OFFICE ACCOMMODATION FOR WORKS MINISTRY
- Oyebanji restates commitment to equipping youths with Innovative, Entrepreneurial Skill
- Oyebanji reinstates commitment to sports development
- Oyebanji at APC Ward meeting, calls for unity, accommodation of new members